Producer, Songwriter and Musician, Emmanuel Adeniran has released a brand new single titled “Mo Wá”.
As Jesus said, “Let the little children come to me, and do not hinder them, for the kingdom of heaven belongs to such as these.”
“The Holy Spirit inspired me to write this song to remind us all that we are all his children and he asks us all to come. This song is an affirmation to the ones who answer this call. I’m grateful to have the vocal talents of my sister Abiola Dosunmu (Lizdos Omooba) on this song”, Emmanuel Adeniran.
STREAM MP3
Song Lyrics
Ọmọ bàbá ni mo jẹ́
Àyìkú nípa ẹ̀jẹ̀ ẹ rẹ̀
Mo di ẹ̀dá títún
NÍtorí ó kú fún mi
O hun àtijọ́ ti kọjá lọ
O hun titun ti dẹ́
Ẹni tí mo jẹ́ tẹ́lẹ̀ ti do o hun Ìgbàgbé
KÍyèsi mo dọmọ titun
Mo wá
Mo wá
Mo wá
Mo bèèrè
Mo bèèrè
Mo bèèrè
Mo kànkùn
Mo ní ìgbàgbọ́ pé ẹ gbó mi
Mo wá
Mo wá
Èmi ọmọ ò rẹ wá
Èmi yìí náà mo ṣákolọ
Mo dẹ̀ ṣe ìfẹ́ inú mi
Èmi yìí náà mo wùwà ìkà
Síbẹ̀sí o forí jì mí
O hun àtijọ́ ti kọjá lọ
O hun titun ti dẹ́
Èmi ọmọ tó kú, tó sì tún yè
Èmi ọmọ tó sọnù tí a sì ríi
Mo wá
Mo wá
Mo wá
Mo bèèrè
Mo bèèrè
Mo bèèrè
Mo kànkùn
Mo ní ìgbàgbọ́ pé ẹ gbó mi
Mo wá
Mo wá
Èmi ọmọ ò rẹ wá
Ẹjẹ́ kọmọdé kó wá o
Ẹjẹ́ kọmọdé kó wá
Ẹjẹ́ kọmọdé kó wá o
Ẹjẹ́ kọmọdé kó wá
Mo wá
Mo wá
Jòjòló ọmọdé kékeré jòjòló
Àwon lọ̀ré elédùmarè
Ẹjẹ́ kọmọdé kó wá
Mo wá
Mo wá
Ẹjẹ́ kọmọdé kó wá o
Ẹjẹ́ kọmọdé kó wá
Ẹjẹ́ kọmọdé kó wá o
Ẹjẹ́ kọmọdé kó wá
Mo wá
Mo wá
Jòjòló ọmọdé kékeré jòjòló
Àwon lọ̀ré elédùmarè
Ẹjẹ́ kọmọdé kó wá
Mo wá
Mo wá
NaijaGospelBeats Naija Gospel Music Hub
